IROYIN YAJOYAJO

Tuesday, 10 March 2026

Gbajugbaja oniṣowo niluu Oṣogbo nni, Ọmọọba Ọbẹlawọ, ti jade laye


Ọmọọba Lawal Ọbẹlawọ, to jẹ gbajugbaja onisowo niluu Oṣogbo, ni wọn ti sọ pe o jade laye bayii.

Inu oṣu karun ọdun yii ni baba naa i ba pe ọmọ ọdun mérindinlọgọrun loke eepẹ.

Oun ni oludasilẹ Lopin Nigeria Limited, o si ni ẹka ni orileede France, Ivory Coast ati UK.

Ilu Ejigbo nipinlẹ Ọṣun ni wọn ti bi Ọmọọba yii, o si bẹrẹ okoowo rẹ ni Abidjan ko too di pe o gbẹrẹgẹdigẹ niluu Oṣogbo.


No comments:

Post a Comment