IROYIN YAJOYAJO

Thursday, 14 May 2026

Dokita Oluṣẹgun Ọṣọba ti ku o


Ọkan lara awọn to kọ iwe ofin orileede Naijiria lọdun 1976, Dokita Samuel Oluṣẹgun Ọṣọba, ti jade laye.


Ninu ile rẹ niluu Ijẹbu-Ode la gbọ pe o ku si nirọlẹ oni Tọsidee.


Ẹni ọdun mejilelaadọrun-un ni baba onkọtan naa k'Ọlọjọ to de.

No comments:

Post a Comment